a
Mk 10.1
;
Lk 17.11
;
Jh 4.40-42
.
b
Mt 10.5
;
Jh 4.4
.
Luke 9:51-52
Ìtakò àwọn ará Samaria
51
a
Nígbà tí ọjọ́ àti gbà á sókè ń súnmọ́, ó pinnu láti lọ sí Jerusalẹmu.
52
b
Ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ lọ sí iwájú rẹ̀. Nígbà tí wọ́n sì lọ wọ́n wọ ìletò kan tí í ṣe ti ará Samaria láti pèsè sílẹ̀ dè é.
Copyright information for
YorBMYO